BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ipinlẹ Oyo
1:01
Orin,
Kò ṣe é má gbọ̀ ọ́
, Duration 1,01
6 Ògún 2026
Obìnrin tó bá rí Olóòlù, ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ yóò gbẹ lorí ìdúró ni, èyí tó bá ya fídíò rẹ̀ bíi Wasilat láì ṣe ìràpadà, yóò kú tàbí ya wèrè láàárín ọjọ́ keje - Ìdílé Olóòlù
4 Ògún 2026
Oriyomi Hamzat kò kópa nínú ìdìbò abẹ́nú Accord, ẹ yọ ọ́ kúrò bíi olùdíje gómìnà - Busari Gudugúdù wọ́ ẹgbẹ́ òṣèlu Accord àti INEC lọ sílé-ẹjọ́
4 Ògún 2026
N kò kú o, ń kò sì ya Oloolu, àlàyé rèé lórí bí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe wáyé - Wasilat
4 Ògún 2026
Ààfin Olubadan fọhùn síta lórí bí orí oyè Lekan Alabi, Abese Olubadan, ṣe sùn ìta
4 Ògún 2026
Tinubu sọ̀rọ̀ fún ìgbà àkọ́kọ́ lórí ìtúsílẹ̀ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ Oriire lákàtà ajínigbé, kókó ohun tó sọ rèé
31 Agẹmo 2026
DSS fi ojú afurasí márùn-ún ba ilé-ẹjọ́ lórí ìjínigbé tó wáyé l'Oyo
30 Agẹmo 2026
Bàálù tí Makinde rà kò lè nípa gidi lórí ètò ààbò l'Oyo, torí kìí ṣe irú bàálù t'awọn ẹ̀ṣọ́ elétò ààbò máa ń lò - Adeyi
30 Agẹmo 2026
Mo wà nínú ilé nígbà táwọn DSS ń yìnbọn lákọ lákọ láti pa mí, àmọ́ wọn ò rí mi - Sunday Igboho
29 Agẹmo 2026
Ìdí tí mo fi pinnu láti má báwọn jàndùkú tó jí ìyàwó mi gbé nílé ẹ̀kọ́ Esinele sọ̀rọ̀ mọ́ - Ọ̀jọ̀gbọ́n Alamu
28 Agẹmo 2026
Wo àwọn ibi tí Egúngún Olóòlù yóò lọ nílùú Ibadan, àwọn ọjọ́ tí yóò wà láwọn agbègbè náà àti ohun márùn ún tó yẹ kí o mọ̀ nípa Egúngún olóòlù
28 Agẹmo 2026
5:16
Fídíò,
Àdó olóró àwọn ajínigbé pa Shuaibu aṣọ́gbóọba lásìkò tó ń lé àwọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé ní Oriire, àwọn ẹbí rẹ̀ pariwo síta
, Duration 5,16
27 Agẹmo 2026
Ẹkún sọ níbí ìsìn ìrántí fún olóògbé John Olaleye olùkọ́ Oriire táwọn jàndùkú ajínigbé ṣekúpa
26 Agẹmo 2026
APC àti Makinde ju òkò ọ̀rọ̀ lu ara wọn lórí ìdájọ́ ilé ẹjọ́ láti dènà EFCC láti ṣe ìwádìí ìṣúná Oyo
24 Agẹmo 2026
Aláànú kan kéde láti ṣe alágbàtọ́ láéláé fún ọmọ mẹ́ta tí John Olaleye bí, olùkọ́ táwọn ajínigbé pa ní Oriire
23 Agẹmo 2026
Lẹ́yìn ìjà tó mú ẹ̀mí èèyàn méjì lọ l'Ojoo, ìjọba Oyo wó àwọn ilé pákó ibẹ̀
18 Agẹmo 2026
Ohun tí a mọ̀ nípa rògbòdìyàn tó wáyé l'Osogbo níbi tí èèyàn méjì ti kú, tí ọ̀pọ̀ tún farapa
17 Agẹmo 2026
Gbogbo ìgbà ti ọmọ mi bá rí àlejò ni ẹ̀rù máa ń bà á báyìí – Ìyá akẹ́kọ̀ọ́ tó gba ìtúsílẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Oyo
17 Agẹmo 2026
Ìjọba, ẹ bá wa ṣètò láti gbé òkú ọkọ mi wálé ká lè sin ín, ẹ sì ràn mí lọ́wọ́ lórí ètò ẹ̀kọ́ àwọn ọmọ rẹ̀ - Ìyàwó John Olaleye
17 Agẹmo 2026
''Ohun tó kàn fáwọn akẹ́kọ̀ọ́ Oríire tó bọ́ lọ́wọ́ ajínigbé rèé, bí bẹ́ẹ̀ kọ́ọ́...''
16 Agẹmo 2026
Wo orúkọ gbogbo àwọn ọmọ ogun àti ọlọ́pàá tó kú sínú ìgbìyànjú láti dóòlà àwọn olùkọ́ àti akẹ́kọ̀ọ́ Oriire
15 Agẹmo 2026
Ọlọ́pàá mú afurasí ajọ́mọgbé méjì n'Ibadan, dóòlà ọmọ ọdùn márùn-un tí wọ́n jí gbé
15 Agẹmo 2026
''Makinde ní láti tọrọ àforíjìn lọ́wọ́ àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé, àjọ UNO tó ń ké pè kò lè sèwádìí ìṣẹ̀lẹ̀ náà''
15 Agẹmo 2026
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa John Olaleye, olùkọ́ Oriire kẹta tí àwọn agbésùnmọ̀mí pa ní àhámọ́?
14 Agẹmo 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology