BBC News, Yorùbá - Ìròyìn
Ìròyìn tó ṣe kókó
Àjọ̀dún Lisabi 2026 gbọ̀rẹ̀gẹ̀jigẹ̀ lóòótọ́, àmọ́, a ṣẹ̀ṣẹ̀ ń mẹ́yẹ bọ̀ lápò ni - Amosun
Liṣabi ni jagunjagun to lewaju awọn Ẹgba kuro niluu Oyo lọdun 1830 lati tẹdo si abẹ Olumo.
Wo ohun tó mú àyájọ́ ọjọ́ ìsinmi 'Palm Sunday' yàtọ̀
Ayajọ yii jẹ ọjọ ti awọn ọmọlẹyin Kristi fi maa n ṣe ami bi Jesu Kristi ṣe gun kẹtẹkẹtẹ wọ Jerusalem nigba to fi wa laye.
Lẹ́yìn ìpàdé àpapọ̀ l'Abuja, wo àwọn tí yóó tukọ̀ APC fọ́dún mẹ́rin
Nibi ipade ọhun ni wọn tun ti yan Alaga apapọ wọn, Nentawe Yilwatda ati Ajibola Basiru pada sipo alaga ati Akọwe apapọ ẹgbẹ APC.
Rògbòdìyàn PDP: Wo àwọn tọ kọ̀yìn sí ìpàdé àpapọ̀ igun Wike tí yóò wáyé l'Abuja lónìí
Pẹlu bi ẹgbẹ PDP ṣe ti pin, ti awọn alaga ẹgbẹ ti ṣe ọtọọtọ, ti ọpọ gomina PDP si ti kuro nibẹ, awọn kan ti sọ pe awọn ko ni i de ibi ipade ti Wike atawọn eeyan rẹ gbe kalẹ yii.
Afẹ́fẹ́ òjò fa ìjàmbá ọkọ̀ ńlá l'Osogbo
Ni deede aago mẹjọ alẹ ọjọ Àbámẹ́ta naa ni ojo to mu afẹfẹ nla dani naa rọ to si ba ọpọlọpọ nnkan jẹ niluu Osogbo.
Agbébọn 38 pàdé ikú lọ́wọ́ ológun Naijiria, wọ́n gba ìbọn AK-47 àti àdó olóró lọ́wọ́ wọn
Ikọ ti a tun a mọ si Operation Hadin Kai naa sọ pe owurọ kutu ọjọ Satide, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu Kẹta ọdun 2026 yii ni awọn mu awọn eeyan naa balẹ.
Agbébọn tó kó òṣìṣẹ́ mẹ́ta lọ nílé ìwòsàn l'Ondo, ohun tí a mọ̀ rèé
Awọn agbebọn naa ya wọ ile iwosan ọhun ni deede aago meji oru ọjọ Abamẹta, ọjọ kejidinlọgbọn oṣu Kẹta ọdun 2026 yii, wọn si ko awọn osisẹ ibẹ mẹta lọ.
Yilwatda wọlé padà bíi Alága àpapọ̀ APC pẹ̀lú àwọn olóyè ẹgbẹ́
Bi wọn ṣe fẹnuko naa ni wọn si bura fun awọn alakoso tuntun yii lẹ́sẹ̀kẹsẹ̀.
'Ìwà ọ̀daràn sí ẹ̀tọ́ ọmọnìyan tó burú jùlọ': Ṣé ó yẹ káwọn orílẹ̀ èdè tó kó ilẹ̀ Africa san owó gbà mábinú?
Igbimọ aṣofin aajọ ìṣọkan agbaye ti buwọlu kikede fifi awọn eeyan ṣe ẹru gẹgẹ bi iwa ọdaran to buru julọ ti wọn ṣe lati fi tẹ ẹtọ awọn eeyan mọlẹ. Nibi ifẹnuko naa ti wọn ti rọ gbogbo awọn orilẹ ede to ko awọn eeyan lẹru lati da awọn ohun ini awọn eeyan bẹẹ ti wọn ji ko pada.
Wo bí Naijiria, Egypt ṣe ń pàdánù lẹ́ka epo nítorí ogun Iran, tí nǹkan sì ń ṣe ẹnu ire fún South Africa
Ogun Iran mu ayipada ba iye owo epo ati bi wọn ṣe n gbe epo wọlu, o ko Naijiria ati Egypt ni papamọra ṣugbọn o n la ọna miran ti wọn le gba nipasẹ South Africa.
Ayẹyẹ ọdún Lisabi gbérasọ ní ìlú Abeokuta pẹ̀lú àwọn àkọ̀tun àrà
Bo tilẹ jẹ pe lati ọjọ Aje, ọsẹ yii, ni ayẹyẹ naa ti bẹrẹ pẹlu oniruuru eto ọlọkan-o-jọkan ti wọn ti la kalẹ, ṣugbọn oni ọjọ Abamẹta, ọjọ Kejidinlọgbọn, oṣu Kẹta ni aṣekagba eto naa, nibi ti awọn eeyan pataki ti wọn ti ṣe bẹbẹ ni oniruuru ẹka ti peju lati kopa.
ICPC tú El-Rufai sílẹ̀ lẹ́yìn tó pàdánù ìyá rẹ̀
Èyí ló ń wáyé lẹ́yìn tí ìròyìn gbòde pé El-Rufai pàdánù ìyá rẹ̀, Hajiya Umma El-Rufai ní ọjọ́ Ẹtí ní ìlú Cairo, orílẹ̀ èdè Egypt.
Móríwú
BBC News Yorùbá ti wà lórí ìkànnì WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ìròyìn Àkàgbádùn
Àjọ Ìṣọ̀kan Àgbáyé, orílẹ̀èdè 123, bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ tí yóò sọ òwò ẹrú di ìjìyà tó burú jù lọ fún ọmọnìyàn
Igbesẹ ti awọn orilẹede 123 ti fọwọ si yii, awọn ilu bii America, Israel ati Argentina sọ pe awọn ko fara mọ ọn ni tawọn.
Wo bí ìgbẹ́jọ́ àwọn afurasí méje tó dáná sun ilé Asabi Olórìṣà n'Ilọrin ṣe lọ
Asabi Olorisa ni olujẹjọ keji ti sọ fun oun tẹlẹ pe awọn ti fẹ le oun ni Ilọrin tẹlẹ ṣugbọn tori pe oun ti kọle ni lawọn o ti fii ṣe bẹẹ.
Àwọn jàndùkú agbébọn ṣekúpa sọ́jà mọ́kànlá, ọlọ́pàá kan, Gómìnà ṣàtìlẹ́yìn ìrànwọ́ fáwọn ẹ́bí olóògbé
Lalẹ ọjọ Iṣẹgun ọsẹ yii ni iṣẹlẹ ọhun ṣẹlẹ ni Giro Masa ni ijọba ibilẹ Shanga ni ipinlẹ Kebbi.
Àlàyé lórí ọ̀nà tuntun tí Amẹrika fẹ́ gbà láti fìyà jẹ orílẹ́èdè Iran
Awọn onwoye sọ pe Amẹrika n gbero lati gbẹsẹ le erekusu Kharg Island nibi ti Iran n ko epo rọbi ti wọn n ta silẹ okeere pamọ si.
Àwọn agbésùnmọ̀mí tó jí ọmọ ìjọ ECWA mẹ́jọ gbé ní Kwara ń bèèrè bílíọ̀nù kan náírà fún ìtúsílẹ̀ wọn
Eniọwọ Timothy Omole ijọ ECWA salaye pe ẹrọ ibanisọrọ ọkan lara awọn ti wọn ji gbe ni wọn lo lati fi pe
Àwọn jàndùkú ya wọ ọ́fíìsì Amotekun l'Osun, jí ìbọn wọn gbé sálọ
Abiodun Ojelabi to jẹ alukoro fun awọn ọlọpaa ipinlẹ Osun ṣalaye pe iroyin naa ti de eti awọn, awọn si ti bẹrẹ iwadi lori ọrọ naa.
NBA,Ẹgbẹ́ Amòfin Naijiria bínú sí Sowore tó pàtẹ ìpàdé akọ̀ròyìn nínú kóòtù
Ilu Abuja ni iṣẹlẹ naa ti waye lanaa ọjọ Iṣẹgun, nile ẹjọ giga kan.
'Biola Bayo, mo fà ẹ́ sí kóòtù Ọlọ́run'-Princess bú sígbe torí Baba Ijesa tí Biola Bayo gbé wá sóri ètò
Lori ifọrọwerọ naa ni Princess fi tun sọ pe Ọlọrun yoo ṣedajọ fun Biola ati Ijesa, to ba jẹ pe bi eeyan ṣe n ṣe ni wọn ṣe yẹn.
Ohun tó máa ṣẹlẹ̀ sí ẹni tí kò bá dìbò fún Tinubu lọ́dún 2027 rè é - Portable
Nínú fídíò kan tí akọrin náà gbé sójú òpó Instagram rẹ̀ ló ti ń sọ àwọn ọ̀rọ̀ àlùfàńṣà, tó sì ń sọ̀rọ̀ sí àwọn tí kò bání dìbò fún Tinubu lọ́dún 2027.
Èmi ṣì ni alága NURTW- MC Oluomo
Ṣáájú ni ìròyìn tí kọ́kọ́ gbòde pé Baruwa àti àwọn èèyàn rẹ̀ yawọ ilé ẹgbẹ́ NURTW tó wà ní Abuja tí wọ́n sì fẹ́ àkóso ilé ẹgbẹ́ náà pé òun ni ilé ẹjọ́ dájọ́ pé òun ó jẹ́ ojúlówó alága ẹgbẹ́ náà.
Mo tọrọ àforíjì lọ́wọ́ ẹ̀yin ọmọ Naijiria fún iná ọba tí kò sí lásìkò yìí- Adelabu
Adelabu ṣo pe oun paapaa mọ pe ai si ina ọba deede yii n ṣe akoba pupọ fun ọrọ aje awọn eeyan, ka ma ti i sọ ti ooru buruku to n mu lasiko yii lai ṣiwọ.
Fídíò, Mo ti bí ọmọ márùn-ún tẹ́lẹ̀ kí n tó bí ibẹ́rin báyìí, ìbejì ni scan sọ fún mi- Ìyá Ìbẹ́rin, Duration 4,35
Nigba ti mo gbọ pe iyawo mi bi ọmọ mẹrin, ẹ ru ba mi, mo si fẹ ṣalọ- Baba Ibẹrin
Ìròyìn Pàtàkì
Ẹ tẹ̀lé wa lórí ìkànnì ayélujára
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
À n ṣiṣẹ́ kárakára láti dáàbò bò àwọn èèyàn Kwara- Kọmiṣọnna ọlọ́pàá Kwara
Olori ọdọ ilu naa, Baloude Najeem ti BBC Yoruba ba sọrọ lori ago sọ pe nnkan bi aago mẹjọ aarọ ni iṣẹlẹ naa waye.
Ìdí rèé tí àpapọ̀ ẹgbẹ́ òṣìṣẹ́ NLC, TUC, NULGE àti JNC fi fagilé ìfẹ̀họ́núhàn tí wọ́n fẹ́ ṣe tako bánkì UBA l'Osun
Lọsẹ to kọja ni awọn agbarijọpọ ẹgbẹ oṣiṣẹ ipinlẹ Osun ti kede pe ifẹhonuhan naa yoo waye ni ọjọ kẹrinlelogun osu yii lori bi ile ifowopamọ UBA ṣe kọ lati gbẹsẹ kuro lori owo ijọba ibilẹ to wa ni akata wọn.
Wo àwọn orílẹ́ède tó ń jèrè àtàwọn tó ń wọ gbèsè lórí ogun Iran àti Amẹrika pẹ̀lú Israel tó ń lọ
O ti han gbangba pe bi Amẹrika ati Israel ṣe n ju ado oloro si Iran ti Iran naa si n da a pada si Israel ati sawọn ibudo ologun Amẹrika to wa ni ẹkun Middle East ti ṣakoba fun ọrọ aje ọpọ orilẹede.
Fídíò, Inú abala àríwísí làwọn olólùfẹ́ mi ti tẹ orúkọ 'Arike Pre order' mọ́ mi – Arike Pre order, Duration 3,07
Ọgbẹni Samuel Banks ti ọpọ mọ si Arikẹ Pre Order lori ayelujara naa sọ pe, Fídíò àwàdà mi wà láti jẹ́ káwọn èèyàn mọ̀ pé bí wọ́n bí èèyàn nínú ẹrọ̀fọ̀ kò ní kó máà jéèyàn láyé.
Àwọn agbébọn kọlu ìjọ ECWA ní Kwara, wọ́n jí èèyàn mẹ́jọ gbé.
Iṣẹlẹ naa waye lanaa ọjọ Aiku ọjọ kejilelogun Oṣu kẹta ọdun 2026 ni ile ijọsin ECWA to wa ni ilu naa ni nnkan bi ago mẹwa owurọ.
Kò tí ì sí obìnrin kankan tó jáde síta pé wọ́n fipá bá òun lòpọ̀ lásìkò ọ̀dun Ozoro - Iléeṣẹ́ ọlọ́pàá
Ọpọ fidio lo ti kun ori ayelujara, eyi to ṣafihan bi awọn ọdọ ọkunrin ṣe n kọlu awọn obinrin ti wọn da wa.
Ọ̀dọ́kùnrin ẹni ọdún 21 fipá bá obìnrin lopọ̀, fún un lọ́rùn pa l'Ondo
Awọn olugbe ilu naa ko mọ ọjọ ori oloogbe naa, sugbọn wọn salaye pe obinrin agbalagba ni obinrin ti Alabi Anthony fi ipa ba lopọ.
Makinde kéde ₦10,000 owó ìrànwọ́ fáwọn òṣìṣẹ́ ìpínlẹ̀ Oyo torí ọ̀wọ́ngógó epo bẹntiróòlù
Makinde ṣalaye pe awọn oṣiṣẹ yoo ri owo yii gba fun oṣu mẹta na lati maa fi wọ ọkọ lọ sibi iṣẹ wọn.
Bode Thomas, ọlọ́pọlọ pípé, aṣaájú àmọ́ tó ní inú fùfù
Bi Olabode Thomas ko tilẹ dagba tabi darugbo ko to jade laye, nitori ko lo ju ọdun mẹrinlelọgbọn lọ, to fi tẹri gbasọ, sibẹ a ko gbọdọ gbagbe akanda ọmọ Yoruba yii, tori ipa to ko si idagbasoke iran Yoruba ati Naijiria lapapọ.












































































