BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Aabo orile-ede
Ṣé lóòótọ́ làwọn agbébọn tún yawọ ìlú Ogbomoso? Àlàyé rèé
19 Èbibi 2026
Ọlọ́pàá ṣàlàyé bí àwọn alamí ṣe ran àwọn ajínigbé tó kọlu iléẹ̀kọ́, jí akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ gbé l'Oyo lọ́wọ́
19 Èbibi 2026
Gómìnà Seyi Makinde ní ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo ṣetán láti jíròrò pẹ̀lú àwọn agbébọn tó jí akẹ́kọ̀ọ́, olùkọ́ gbé kí wọ́n lè tètè padà wálé
19 Èbibi 2026
"Agbekoya ní agbára ìbílẹ̀ láti lé àwọn jàndùkú afẹ̀míṣòfò kúrò ní gbogbo ilẹ̀ Yoruba láàrin oṣù kan péré, àmọ́..."
19 Èbibi 2026
Àwọn agbébọn mẹ́ẹ̀dógún ya wọ agboolé táwọn ilégbèé wà ní Ijebu-Ode, jí èèyàn mẹ́ta gbé lọ
13 Èbibi 2026
Ẹgbẹ́ alákatakítí ISIS, Al Shabaab àti Al Qaeda tí a lé ní Iraq àti Syria, ti fi ìwọ̀ oòrùn Afrika ṣe ibùba – Ìjọba Amẹrika kìlọ̀
13 Èbibi 2026
Lẹ́yìn tí ajínigbé gba N50m owó ìtúsílẹ̀, wọn pa àgbà olóṣèlú lẹ́gbẹ́ ADC, fi òkú rẹ̀ ránṣẹ́
12 Èbibi 2026
Ṣé lóòótọ́ ni àdó olóró tí ológun Chad jù fún Boko Haram pa ọ̀pọ̀ apẹja ọmọ Naijiria?
12 Èbibi 2026
Amotekun nawọ́ gán afurasí agbéṣùmọ̀mí ní ìpínlẹ̀ Ondo
9 Èbibi 2026
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ikọ̀ ọlọ́pàá VCRU tuntun, ìdí fún ìdásílẹ̀ rẹ̀ àti iṣẹ́ àwọn ọlọ́pàá náà
8 Èbibi 2026
Àwọn ajínigbé tún jí òṣìṣẹ́ iléeṣẹ́ iná mọ̀nàmọ́ná IBEDC gbé, àwọn aláṣẹ ké gbàjarè síta
4 Èbibi 2026
3:25
Fídíò,
Wọ́n pe pásítọ̀ kó wá ṣe ìṣọ́ òru ní ṣọ́ọ̀ṣì ni káwọn agbébọ̀n tó yìnbọn paá – Aráàlú sọ̀rọ̀ lórí ìkọlú àwọn agbébọn sí ṣọ́ọ̀ṣì kan l'Ekiti
, Duration 3,25
4 Èbibi 2026
''Ọlọ́pàá lu kóndó mọ́ ọlọ́kadà lórí'' ní Iseyin; ọlọ́kadà kú, aráàlú fẹ̀hónúhàn
3 Èbibi 2026
Ẹbí ọlọ́kadà tó kú n'Ibadan lẹ́yìn táwọn ọlọ́pàá dá a dúró ké gbàjarè, iléeṣẹ́ ọlọ́pàá ṣàlàyé nǹkan tó ṣẹlẹ̀
2 Èbibi 2026
Bíjọba Tinubu kò ṣe rẹ́yìn ikọ̀ afẹ̀jẹ̀wẹ̀ tó ń pa Krísítẹ́ní, a ti gé ìrànwọ́ wa sí Naijiria dé ìdajì - Amẹ́ríkà
30 Ìgbé 2026
Ọlọ́pàá "yìnbọn pa" ọkùnrin kan níta gbangba lórí fídíò tó gba orí ayélujára, aráàlú fọnmú
29 Ìgbé 2026
Ìṣọ́ òru di ibùdó ẹ̀jẹ̀ níjọ CAC Eda Oniyo l‘Ekiti, agbébọn pa pásítọ̀, jí ọ̀pọ̀ ọmọ ìjọ gbé lọ
29 Ìgbé 2026
Aiyedatiwa jẹ wá lówó oṣù mẹ́fa, ó tún fẹ́ lé wa níbi tí ìrandíran wa ń gbé láti 1943 - Àwọn àkàndá ẹ̀dá Ago Ireti figbeta l'Ondo
25 Ìgbé 2026
4:29
Fídíò,
Oògùn ni àwọn darandaran kọ́kọ́ fi na ọkọ mi kí wọ́n tó ṣa wẹ́lẹwẹ̀lẹ - Ìyàwó Oloye tí darandaran pa n'Ibadan
, Duration 4,29
24 Ìgbé 2026
Oògùn ni àwọn darandaran kọ́kọ́ fi na ọkọ mi kí wọ́n tó ṣa wẹ́lẹwẹ̀lẹ - Ìyàwó Oloye tí darandaran pa n'Ibadan
24 Ìgbé 2026
Kí ló ṣẹlẹ̀ tí ọ̀gá ọlọ́pàá 167 fi ń sọ tẹnu wọn níwájú ìgbìmọ̀ tó ń ṣèbáwí ọlọ́pàá? Àlàyé rèé
22 Ìgbé 2026
Ìdí rèé tí a fi ń ra màálù kan ní ₦2.5m báyìí, àwọn alápatà sàlàyé
20 Ìgbé 2026
Ṣé lóòótọ́ ni pé ìdìbó 2027 tó ń bọ̀ ló jẹ́ kí ètò ààbò mẹ́hẹ ní Naijiria? Ohun tí a mọ̀ rèé
19 Ìgbé 2026
Agbébọn pa ọkùnrin kan lọ́nà oko, jí ìyá ìyàwó tuntun àtàwọn mí-ìn gbé lọ ní Kwara
17 Ìgbé 2026
Page
1
nínú
40
1
2
3
4
5
6
7
40
Tókàn
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology