BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Wo àwòrán Ọmọọba Harry àti Ìyàwó rẹ̀ nígbà tí wọ́n dé sí Naijiria
Àkọlé àwòrán,
Ọmọọba Harry pẹlu Iyawo rẹ lasiko ti wọn ṣe abẹwo si Naijiria
Published
11 Èbibi 2024
Àkọlé àwòrán,
Awọn eeyan n ya fọtọ pẹlu Ọmọọba Harry ati Iyawo rẹ Meghan, ti wọn si n ki wọn kaabọ
Àkọlé àwòrán,
Wọn fi ilẹkẹ da Ọmọọba Harry ati Iyawo rẹ Meghan lọla lati bu ọwọ fun wọn gẹgẹ bii eeyan nla
Àkọlé àwòrán,
Gomina ipinlẹ Kanduna, Uba Sani ati Ọmọọba Harry nigba to ba lẹ si ipinlẹ Kaduna, ti wọn si tun fi aṣọ agbada nla da lọla.
Àkọlé àwòrán,
Awọn onijo ibilẹ fi ijo da Ọmọọba ati iyawo rẹ lara ya lasiko abẹwo.
Àkọlé àwòrán,
Gomina Uba Sani ati Ọmọọba Harry ni ile ijọba ipinlẹ Kaduna
Àkọlé àwòrán,
Ọmọọba Harry ati Gomina ipinlẹ Kaduna n wo bi awọn onijo ṣe n fi ijo da wọn lara ya ni ile ijọba ipinlẹ Kaduna
Àkọlé àwòrán,
Awọn onilu ni ile ijọba
Àkọlé àwòrán,
Awọn olorin ibilẹ n fi orin da Ọmọọba lọla.
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
04:05
Fídíò,
Mo ti fẹ́ obìnrin rí lágbo tíátà àmọ́ kò ní àṣeyọrí, owó, obìnrin àti agbára ló ń fa gbajúmọ̀ ọkùnrin ṣubú - Abayomi Alvin
, Duration4,05
01:02
Fídíò,
Sola Sobowale àti Lateef Adedimeji sọ̀rọ̀ lórí àmì ẹ̀yẹ AMVCA tí wọn gbà
, Duration1,02
05:59
Fídíò,
Ṣọ́ọ̀ṣì kan rèé tí wọn kií lanu sọ̀rọ̀, ọwọ́ lásán làwọn akọrin, oníwàásù àti olùjọ́sìn fi ń júwe
, Duration5,59
00:52
Fídíò,
Àwọn aṣọ aláràmbarà tí wọ́n lò níbi ayẹyẹ AMVCA
, Duration0,52
03:29
Fídíò,
"Eré ìdárayá ìgbátí ni mo fi ń jẹun, wọ́n ti gbá mi léti rí tí ojú mi ya, mo sojú Nàíjíríà nínú ìdíje àgbáyé"
, Duration3,29
01:30
Fídíò,
"Iṣẹ́ tóo yàn láàyò lè ṣàkóbá fún ìlera ọpọlọ rẹ lọ́jọ́ alẹ́"
, Duration1,30
01:36
Fídíò,
Ìwádìí BBC tú àṣírí àwọn tó ń fi ajá tó ṣèse lú jìbìtì gbowó lórí ayélujára
, Duration1,36
03:25
Fídíò,
Wọ́n pe pásítọ̀ kó wá ṣe ìṣọ́ òru ní ṣọ́ọ̀ṣì ni káwọn agbébọ̀n tó yìnbọn paá – Aráàlú sọ̀rọ̀ lórí ìkọlú àwọn agbébọn sí ṣọ́ọ̀ṣì kan l'Ekiti
, Duration3,25
01:13
Fídíò,
Ìdí rèé tí ọ̀dà tí o fi ń kun irun rẹ sí àwọ̀ mìràn ṣe lè fa jẹjẹrẹ ọyàn fún ọ
, Duration1,13
03:19
Fídíò,
"Igede Ekiti ni ilé Osun, omi rẹ̀ sàn dé Osogbo ni, ohun tó mú u yíra padà kò di odò ńlá rèé"
, Duration3,19
01:59
Fídíò,
Ǹ jẹ́ ẹ mọ nípa Ọdún Ẹlẹ́gba Èjìwà l‘Eko níbi tí takọ-tabo kìí wọ aṣọ tàbí bàtà?
, Duration1,59
01:41
Fídíò,
Ìjà ìlú wa là ń gbè, a gbà, tí ẹ bá ní à ń ṣe ìwà ipá sáwọn àjèjì - Àwọn ọmọ South Africa ṣe ìwọ́de
, Duration1,41
04:52
Fídíò,
"Ìdí rèé tí mo ṣe fi àkàrà òyìnbó mọ ṣọ́ọ̀ṣì kàtídírà ńlá, èyí tó jẹ́ ìyanu fún ọ̀pọ̀ èèyàn"
, Duration4,52
Ìròyìn tó ṣe kókó
Ariwo ayọ̀ ní ààfin Ooni ti Ile Ife bí Olori Mariam ṣe bí ìbejì ọkùnrin
wákàtí 2 sẹ́yìn
Ilé ẹjọ́ ju pásítọ̀ sí ẹ̀wọ̀n gbére fún bíbá ọmọdé mẹ́ta lò pọ̀, ó tún ṣẹ́ oyún fún wọn
wákàtí 2 sẹ́yìn
Gómìnà Seyi Makinde kéde pé òun yóò dupò ààrẹ Naijiria ni 2027
14 Èbibi 2026
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
Lateef Adedimeji, Oboz, àtàwọn òṣèré míì tó gbàmì ẹ̀yẹ ní AMVCA 2026
10 Èbibi 2026
EFCC kéde wíwá Sadiya Farouq, mínísítà tẹ́lẹ̀ fún ètò ìbojú-àánú wo aráàlú
10 Èbibi 2026
Ẹgbẹ́ NDC kéde ipò ààrẹ sí Gúúsù Naijiria ní 2027, 2031 fún Àríwá
9 Èbibi 2026
Kí ló dé tí ọ̀pọ̀ àwọn tó ń bá Gómìnà Seyi Makinde ṣiṣẹ́ níjọba ìpínlẹ̀ Oyo ń kọ̀wé fipò sílẹ̀?
9 Èbibi 2026
Lateef Adedimeji kéde orúkọ àwọn ìbẹ́ta rẹ àti ọjọ́ tí wẹ̀jẹwẹ̀mu ìdúpẹ́ yóò wáyé
9 Èbibi 2026
Ta ni Stanley Osifo tó fẹ́ kojú Tinubu níbi ètò ìdìbò abẹ́nú APC?
9 Èbibi 2026
Amotekun nawọ́ gán afurasí agbéṣùmọ̀mí ní ìpínlẹ̀ Ondo
9 Èbibi 2026
Ta ló ń wó pátákó ìpolongo Gómìnà Adeleke lulẹ̀ l'Osun tí APC àti Accord Party fi ń ju òkò ọ̀rọ̀ sí ara wọn?
9 Èbibi 2026
Kí ló fa òórùn àbaadì tó kó aráàlú lọ́kàn sókè l'Ado Ekiti? Àlàyé rèé
9 Èbibi 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Ariwo ayọ̀ ní ààfin Ooni ti Ile Ife bí Olori Mariam ṣe bí ìbejì ọkùnrin
2
Ooni Ile Ife, Adeyeye Ogunwusi sọ ìdí tó fi fẹ́ ìyàwó púpọ̀
Tí a mú dójú ìwọ̀n gbẹ̀yìn ní: 10 Ọ̀pẹ̀̀ 2022
3
Ilé ẹjọ́ ju pásítọ̀ sí ẹ̀wọ̀n gbére fún bíbá ọmọdé mẹ́ta lò pọ̀, ó tún ṣẹ́ oyún fún wọn
4
Ajínigbé fi ayédèrú iṣẹ́ tàn mi lọ sí Zamfara, wọ́n tún fowó ọkọ̀ ránṣẹ́ kí n lè tètè wá - Akẹ́kọ̀ọ́jáde Fásitì
5
Gómìnà Seyi Makinde kéde pé òun yóò dupò ààrẹ Naijiria ni 2027
6
Àwọn ọmọ Nàìjíríà máa fi ojú àwọn olóṣèlú dánrin níbi ètò ìdìbò tó ń bọ̀ - Seyi Makinde
7
Ohun tó yẹ kí o mọ̀ bí Trump ṣe ń ṣàbẹ̀wò sí Ààrẹ Xi ní China
8
Ọ̀pọ̀ èrò n‘Ibadan fẹ̀sùn ajínigbé kan Dókítà kan, wọ́n fẹ́ lú ú pa, dáná sun ọkọ̀ rẹ̀, ọ̀pẹ́ ọlọ́pàá tó dé sásìkò
9
Mariam Anako: Ohun tó yẹ kí ẹ mọ̀ nípa ìyàwó Ọọni tuntun
Tí a mú dójú ìwọ̀n gbẹ̀yìn ní: 7 Owewe 2022
10
Àwọn agbébọn mẹ́ẹ̀dógún ya wọ agboolé táwọn ilégbèé wà ní Ijebu-Ode, jí èèyàn mẹ́ta gbé lọ
More:
News
•
Sport
•
Weather
•
Worklife
•
Travel
•
Future
•
Culture
•
World
•
Business
•
Technology
•
Science_and_environment
•
Entertainment_and_arts
✕