BBC News,
Yorùbá
Fò kọjá sí nnkan tí ó wà nínú rẹ̀
Ìròyìn
Wò
Gbọ́
Àwọn abala
Ìròyìn
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Idibo Naijiria 2027
Eré ìdárayá
Èyí to gbajúmọ̀ jù
Ojude Ọba 2019: Àwọn èèkàn lórílẹ̀-èdè Nàìjíríà ti péjú fún ayẹyẹ ojúde Ọba
Àkọlé àwòrán,
Ojude Oba tí ọdún yìí ti gbéra sọ pẹ̀lú oníruuru àwọn aṣọ alárànbara yorùba to ń wúni lóri, Awọn ẹgbẹ́ Tobalàṣẹ obinrin rèé nínú àṣọ okè aláwọ̀ ewé
Published
13 Ògún 2019
'Kò sí ohun tó burú nínú bí Ajimobi ṣe dá Yewande tó pa ọkọ rẹ̀ sílẹ̀'
Àwọn Fadá mẹ́rin gbà itusílẹ̀ lọwọ àwọn ajínigbé
Samuel Okwaraji: Ó pé ọgbọ̀n ọdún tí lónìí ti akọni àgbábọ̀ọ̀lù papo dà
Ẹ ṣe àwárí ọdànran tó bọ mọ́ọ yín lọ́wọ́ - Turkur Buratai
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Àkọlé àwòrán,
Lẹ́gbẹ́ lẹ́gbẹ́ ni gbogbo àwọn ti wọ́n péju síbi ayéyé Ojude Oba tí ọdún 2019
Àkọlé àwòrán,
Tokùnrin tobinrin ló wọsọ ìgbà níbi àyẹyẹ ojude oba tọdún yìí, Ẹgbẹ́ Bọbakẹ́yẹ Ọkunrin ni àwọn yìí
Àkọlé àwòrán,
Tarúgbó tomidàn ló wà nibi àyẹyẹ yìí, gbogbo oju wọ́n lo gúrégé pèlú, àwọn ẹgbẹ́ bọ́bakẹ́yẹ obinrin rèé
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn olóyè àti èèkàn ìlú ló péjú
Àkọlé àwòrán,
Kìí ṣe àwọn ẹgbẹ́ gbẹ́ jọdá nìkàn ló péju, àwọn ọdọ náà jáde wá láti yẹ́ àṣ]a ìbílẹ̀ sí
Àkọlé àwòrán,
Aláàfin Ọyọ, ikú bábá yèyé, Ọba Lamidi Adeyemi náà péjú síbi ayẹyẹ ojúde Oba ní'lú Ijebu
Àkọlé àwòrán,
Gómínà ìpínlẹ̀ Ogun, Dapo Abiodun àti Awùjalẹ̀ Ijẹ̀bú Ọba Sikiru Adetona
Àkọlé àwòrán,
Gómìnà tẹ́lẹ̀rí ní ìpínlẹ̀ Ogun, Ọtunba Gbẹnga Daniels
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Bọ́baguntẹ ilẹ̀ Ijẹbu
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo ojú tó ti ríra típẹ tún ni àànfàni láti ṣe "Ẹ k;u àti"
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Obafunwaji Obinrin Adedoyin rèé nínú aṣọ ofi aláwọ̀ búlù
Àkọlé àwòrán,
Ẹgbẹ́ Tobalaṣẹ Ọkunrin náà ko gbẹ́yìn
Àkọlé àwòrán,
Gbogbo àwọn ọmọ ẹgbẹ́ Gbobaniyi lókùnrin àti lóbìrin ló ti lọ ki ọba aláde lóri ìjòkò
Skip Móríwú and continue reading
Móríwú
Àwọn àmúyẹ fun gbígbọ́ orin ko le ṣiṣẹ lori ẹ̀rọ rẹ
01:46
Fídíò,
Líla ọwọ́ sí àwọn ẹbí àti ọ̀rẹ́ rẹ lè jẹ́ kí ẹ̀mí ré gùn - Ìwádìí
, Duration1,46
03:29
Fídíò,
Ìjọba Aiyedatiwa fẹ́ lé wa kúrò ní Agọ Ireti, ó tún kọ̀ láti fún wa ní owó oṣù wa – Àwọn olùgbé Agọ Ireti
, Duration3,29
02:38
Fídíò,
Abula: Eré ìdárayá tiwantiwa tí wọ́n fi orúkọ àmàlà, gbẹ̀gìrì àti ewédú sọ tó ti wá ń di gbajúmọ̀ káàkiri
, Duration2,38
04:55
Fídíò,
Ẹ má sá fún ọmọ ẹlẹ́gbẹ́, ẹnikẹ́ni tó bá fẹ́ wọn yóò là – Ifatolani Ayoka, Olórí emèrè ṣàlàyé
, Duration4,55
05:47
Fídíò,
Ademola Adeleke àti APC sọ̀kò ọ̀rọ̀ sí ara wọn lẹ́yìn ìjà òṣèlú tó wáyé l'Osun
, Duration5,47
01:13
Fídíò,
Ìdí mẹ́rin tí nǹkan ọkùnrin ṣe máa ń nàró ní àárọ̀ tí wọn bá jí
, Duration1,13
05:36
Fídíò,
"Àwọn agbébọn tó ń jà fún ẹ̀sìn gan ń lo òògùn ìbílẹ̀, ṣé ìjọba le fi 1000 Kùránì àti 1m Bíbélì jagun agbébọn báyìí?"
, Duration5,36
03:47
Fídíò,
Ó pẹ́ tí mo ti sá kúrò nílé, mo rán ara mi ní fásitì, ọjọ́ kan làwọn òbí mi rí mi lórí Tẹlifísàn bíi gbajúmọ̀ akọrin - Shodey
, Duration3,47
03:05
Fídíò,
"Ìdájọ́ ikú tí wọ́n dá fún àwọn tó kọlu ṣọ́ọ̀ṣì Owo kò dá ọmọ mi àti àbúrò mi méjì tí wọ́n pa padà"
, Duration3,05
01:27
Fídíò,
Bí o bá ń pẹ́ kí o tó sùn lálẹ́, ewu ń bẹ fún ìlera ọpọlọ rẹ
, Duration1,27
04:11
Fídíò,
Bàbá mi ló pàṣẹ fún mi lójú àlá pé kí n máa múra bí ọkùnrin – Funmilayo Elemure Ogunyemi
, Duration4,11
00:37
Fídíò,
Aráàlú fárígá, ṣèwọ́de ní Ibadan tako ìjọba lórí bí àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àti olùkọ́ tí wọ́n jí gbé ṣì ṣe wà ní àhámọ́
, Duration0,37
End of Móríwú
Ìròyìn tó ṣe kókó
Olóòtú ìjọba UK, Keir Starmer kọ̀wé fipò sílẹ̀
22 Òkùdu 2026
Sunday Igboho ti wọnú igbó bíi ẹ̀ẹ̀mẹrin, a kò tíì rí àwọn tí wọn jí gbé, ₦150m táwọn ajínigbé bèèrè là ń wá - Ọba Igboho
22 Òkùdu 2026
Kí ló fà á tí àwọn ọkùnrin fi máa ń lá àlá ìbálòpọ̀?
22 Òkùdu 2026
Ìwádìí kíkún lóríi kókó ìròyìn
A ti mú afurasí ọ̀daràn tó gé orí ọmọ ni Idanre, ìwádìí ti bẹ̀rẹ̀- Ọlọpaa Ondo
19 Òkùdu 2026
Ìgboro dàrú n'Ilorin lẹ́yìn ìròyìn tó tàn kálẹ̀ pé àwọn agbébọn ti ya wọ àwọn ilé ẹ̀kọ́, ọlọ́pàá kìlọ̀
18 Òkùdu 2026
"Ọlọ́run kò dàbí ènìyàn," mínísítà fún epo rọ̀bì tẹ́lẹ̀ sọ̀rọ̀ sókè lẹ́yìn tí ilé ẹjọ́ ní kò jẹ̀bi ẹ̀sùn rìbá gbígbà tí wọ́n fi kàn án
18 Òkùdu 2026
"Adedibu ò kú o, a sì ń rí Baálẹ̀ Molete"
18 Òkùdu 2026
Òní ni ìdájọ́ àwọn afurasí agbésùnmọ̀mí tó lé ní 400 yóò wáyé l'Abuja
18 Òkùdu 2026
Ìjọba Equatorial Guinea kọ̀wé fipò sílẹ̀ lẹ́yìn tó kùnà láti mú ìlérí rẹ̀ ṣẹ
18 Òkùdu 2026
Inú gbogbo èèyàn ìpínlẹ̀ Osun ló dún sí ìdájọ́ tó fààyè gba Accord láti díje, Adeleke ní wọ́n ń fẹ́ - Ìjọba Osun
17 Òkùdu 2026
Inú ìbànújẹ ọkàn ni mo wà torí àwọn ọmọdé wà ninu awọn èèyàn tawon janduku agbébọn ji gbe, bẹẹ, o ti le ni oṣu kan bayii- Makinde
17 Òkùdu 2026
Àdó olóró agbésùnmọ̀mí ṣekúpa ọlọ́pàá mẹ́ta
17 Òkùdu 2026
Ìròyìn tí àwọn ènìyàn fẹ́ràn jùlọ
1
Kí ló fà á tí àwọn ọkùnrin fi máa ń lá àlá ìbálòpọ̀?
2
Sunday Igboho ti wọnú igbó bíi ẹ̀ẹ̀mẹrin, a kò tíì rí àwọn tí wọn jí gbé, ₦150m táwọn ajínigbé bèèrè là ń wá - Ọba Igboho
3
Mọ̀ nípa ìbejì Oguntoye tí wọ́n fẹ́ ìbejì ọmọ ìyá kan náà
4
Ṣé òótọ́ ni pé ajínigbé tu aláboyún àtàwọn ọmọ rẹ̀ sílẹ̀ lẹ́yìn tí Sunday Igboho fún wọn ní gbèdéke wákàtí méjì?
5
Amẹrika fòpin sí ìrànwọ́ rẹ̀ láti gbógun ti àrùn HIV/AIDS ní South Africa
6
Olóòtú ìjọba UK, Keir Starmer kọ̀wé fipò sílẹ̀
7
Biodun Oyebanji jawe olubori nínú ìdìbò gómìnà ìpínlẹ̀ Ekiti
8
A ti mú afurasí ọ̀daràn tó gé orí ọmọ ni Idanre, ìwádìí ti bẹ̀rẹ̀- Ọlọpaa Ondo
9
"Ilé-iṣẹ́ rédíò Agidigbo FM ni ẹ lè wó, ẹ ò lè wó Oriyomi Hamzat"
10
Ọlọ́pàá gbé Chef Dammy, Sowore àtàwọn míì fapá jánú
Tí a mú dójú ìwọ̀n gbẹ̀yìn ní: 24 Bélú 2023
You might also like:
news
|
sport
|
weather
|
worklife
|
travel
|
future
|
culture
|
world
|
business
|
technology